Chigul

Chioma Omeruah
Chigul in 2019
Ọjọ́ìbíChioma Omeruah
14 Oṣù Kàrún 1976 (1976-05-14) (ọmọ ọdún 50)
Ikeja
Orílẹ̀-èdèNigerian
Orúkọ mírànChigul
Ẹ̀kọ́Delaware State University
Iṣẹ́Teacher, Singer, Comedian, Actress
Gbajúmọ̀ fúnVoices and characters

Chioma Omeruah, tí a mọ̀ orúkọ ìnagi rẹ̀ sí Chigul, jẹ́ apanilẹ́rìn-ín, akọrin, àti òṣèré ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Ó gbajúmọ̀ fún àwọn ipa apanilẹ́rìn-ín rẹ̀ tí ó maá n sábà ṣe ní gbogbo ìgbá

Ìsẹ̀mí rẹ̀

Wọ́n bí Omeruah sí ìlú Èkó. Òun ni àbílé kejì nínu àwọn ọmọ mẹ́rin ti àwọn òbí rẹ̀. Bàbá rẹ̀ ni Samson Omeruah.[1]

Ó lọ sí ilé-ìwé girama méjì kan ní ìlú Jọs àti ní ìlú ìkẹjà,[2] ó sì tún lọ sí ilé-ẹ̀kọ́ gíga Yunifásítì Ìpínlẹ̀ Ábíá fún oṣù mẹ́ta, sááju kí ó tó lọ sí ilé-ẹ̀kọ̀ gíga Delaware State University níbití ó ti kẹ́kọ̀ọ́ ìmọ̀ nípa òfin tó de àwọn ìwà òdaràn.[3][4] Nítorí àìṣedédé rẹ̀ nínu ẹ̀kọ́ náà, ó padà tún kẹ́kọ̀ọ́ èdè Faransé láti ilé-ìwé Delaware State University bákan náà. Ó padà sí Nàìjíríà lẹ́hìn tí ó ti lo ọdún méjìlá ní ilẹ̀ Amẹ́ríkà[5]

Ó kọ́kọ́ di akọrin lábẹ orúkọ C-Flow ṣùgbọ́n orúkọ Chigul bo ti tẹ́lẹ̀ mọ́lẹ̀ lẹ́hìn kíkó àwọn ipa apanilẹ́rìn-ín rẹ̀ nínu àwọn eré. Àkọ́lé àkọ́kọ́ orin rẹ̀ tí ó kọ ni "Kilode", èyí tí ó ṣe pẹ̀lú gbígbohùn rẹ̀ sílẹ̀ tí ó sì pín fún àwọn òrẹ́ rẹ̀.[6] Ó tí kópa nínu eré Nollywood kan tí àkọ́lé rẹ̀ jẹ́ Road to Yesterday.[7]

Àṣàyàn àwọn eré rẹ̀

Àwọn amì-ẹ̀yẹ àti ìfisọ́rí rẹ̀

Odun Aamì-ẹ̀yẹ Ìsọrí Esi Ref
2021 Net Honours Most Popular Media Personality (female) Wọ́n pèé [9]


Àwọn ìtọ́kasí

  1. Watch Chigurl talk about chasing dreams Archived 2015-04-04 at the Wayback Machine., 31 December 2014, Uunista, Retrieved 21 September 2016
  2. The Rise and Rise of Chigul, PremiumTimesNG, Retrieved 20 September 2016
  3. Watch Chigurl talk about chasing dreams Archived 2015-04-04 at the Wayback Machine., 31 December 2014, Uunista, Retrieved 21 September 2016
  4. https://lifestyle.thecable.ng/married-virgin-divorced-chigul/
  5. "Ẹda pamosi". Archived from the original on 2020-10-29. Retrieved 2020-11-21. 
  6. The Rise and Rise of Chigul, PremiumTimesNG, Retrieved 20 September 2016
  7. Badmus, Kayode (10 September 2015). "10 things you should know about Genevieve Nnaji’s upcoming movie, Road to Yesterday". Nigerian Entertainment Today. Archived from the original on 27 September 2016. Retrieved 20 September 2016. 
  8. "Banana Island Ghost Full Cast". Uzomedia. Retrieved 2017-05-20. [Ìjápọ̀ tí kò ṣiṣẹ́ mọ́]
  9. "Net Honours - The Class of 2021". Nigerian Entertainment Today (in Èdè Gẹ̀ẹ́sì). Retrieved 2021-09-07. 

Content Disclaimer

Informasi ini disarikan dari Wikipedia dan disajikan kembali untuk tujuan edukasi. Konten tersedia di bawah lisensi CC BY-SA 3.0. Kami tidak bertanggung jawab atas ketidakakuratan data yang bersumber dari kontribusi publik tersebut.

  1. The information displayed on this website is sourced in part or in whole from Wikipedia and has been adapted for the purpose of restating it. We strive to provide accurate and relevant information, however:
  2. There is no guarantee of absolute accuracy. Wikipedia is an open, collaborative project that can be edited by anyone, so information is subject to change.
  3. It is not intended to constitute professional advice. The content displayed is for informational and educational purposes only. For important decisions (e.g., medical, legal, or financial), please consult a professional.
  4. Content copyright. Wikipedia is licensed under the Creative Commons Attribution-ShareAlike License (CC BY-SA). This means that content may be reused with appropriate attribution and shared under a similar license.
  5. Responsible use. Any risk arising from the use of information from this website is entirely the responsibility of the user.